

?ló?run, Níbo Lo Wá?
A bí Adé?lá ?r?olúwa Adéf?`s?` ní ìpínl?` Ògùn ní oríl?` èdè Nàìjíríà. Ó ?e èwe r?` nínú ay?` àti ìdùnnú. Àw?n òbí r?` àgbà ní ìdílé ìyá ló t?´ ? dàgbà p?`lú ìf?´ tó wàyàmì àti ?`k?´ ìwé tó yè kooro, òun náà sì dara p?` m?´ ?gb?´ ak?rin agbègbè ib?`. ?ùgbó?n n?kan yí bìrí nígbà tí ó kó sí wàhálà ab?´ ilé látàrí ìjìyà tí ó n rí láti ?`d?` ?k? r?`. Inú làásìgbò ìjìyà ara àti ?kàn yìí ló wà tí ó fi pàdánù àw?n ìbejì ?kùnrin r?` méjèèjì tí ó bí ní kògbókògbó.
Nínú ?dún 2019, ?m?kùnrin r?`, àbísìkejì, tí ó fìgbà kan j?´ ?m? ogun ojú omi il?` Am?´ríkà náà tún pa ara r?`. L?´yìn èyí ni Adé?lá tún rí àw?n ?`r?` kòbákùngbé tí ?k? r?` k? nípa r?` sí orí ?`r? ayélujára kà dé ibi pé òun lòun fa ikú ?m? àw?n ?`hún.
Ìrora, ìf?´, àti ìgbàgb?´ Adé?lá fara hàn kedere nínú ìtàn àgb?´gbárímú yìí tí ó gbé kal?` ní ìrètí pé yóò dé etígb?`?´ àw?n tí yóò wúlò fún.
"Nínú ìwé yìí, Adé?lá gbé ìtàn akíkanjú obìnrin kan tí ó dojú k? wàhálà ab?´le kal?`. L?´yìn-ò-r?yìn, p?`lú ìrànl?´w?´ ?ló?run, ó jáwé olúborí." Iloh, Friday Okechukwu (Ph. D)
- Kirjailija
- Adeola Oreoluwa Adefeso
- ISBN
- 9781636031217
- Kieli
- Yoruba
- Julkaisupäivä
- 22.11.2021
- Kustantaja
- Distributed By Ingram Spark
- Formaatti
- Epub - Adobe DRM
- Lue e-kirjoja täällä
- Lue e-kirja mobiililaitteella/tabletilla
- Lukulaite
- Tietokone